Ohun Tí Bíbélì Sọ
Kí ni Bíbélì fi kọ́ni gan-an? Mú ìbéèrè kan nínú àwọn ìbéèrè tó wà nísàlẹ̀ yìí.
Ṣé Ẹnì Kan Wà Tó Rí Ọlọ́run Rí?
Ṣé Bíbélì ta ko ara rẹ̀ ni nígbà tó sọ níbì kan pé ‘kò sí ènìyàn kankan tí ó ti rí Ọlọ́run rí,’ tó sì tún sọ níbòmíì pé Mósè “rí Ọlọ́run Ísírẹ́lì”?
Ṣé Ẹnì Kan Wà Tó Rí Ọlọ́run Rí?
Ṣé Bíbélì ta ko ara rẹ̀ ni nígbà tó sọ níbì kan pé ‘kò sí ènìyàn kankan tí ó ti rí Ọlọ́run rí,’ tó sì tún sọ níbòmíì pé Mósè “rí Ọlọ́run Ísírẹ́lì”?
Ọlọ́run
Bíbélì
Jésù
Ibi Tí Àwọn Ẹni Ẹ̀mí Ń Gbé
Ìyè àti Ikú
Ìyà
Ìgbàgbọ́ àti Ìjọsìn
Ìgbésí Ayé àti Ìwà Rere
Kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Lọ́dọ̀ Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà
Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì?—Èyí Tó Gùn
Bíbélì ń ran ọ̀pọ̀ mílíọ̀nù èèyàn kárí ayé lọ́wọ́ láti rí ìdáhùn sí àwọn ìbéèrè pàtàkì nípa ìgbésí ayé. Ṣé ìwọ náà á fẹ́ jẹ́ ọ̀kan lára wọn?
Báwo La Ṣe Máa Ń Ṣe Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì?
Níbi gbogbo kárí ayé làwọn èèyàn ti mọ àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà mọ́ ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì tí wọ́n máa ń ṣe fáwọn èèyàn lọ́fẹ̀ẹ́. Wo bí wọ́n ṣe máa ń ṣe é.
Ṣé O Fẹ́ Ká Wá Ẹ Wá
O lè mọ̀ sí i nípa Bíbélì tàbí àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà.