Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Lẹ́tà sí Àwọn Ará Éfésù

Orí

1 2 3 4 5 6

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

  • 1

    • Ìkíni (1, 2)

    • Àwọn ìbùkún tẹ̀mí (3-7)

    • À ń kó ohun gbogbo jọ nínú Kristi (8-14)

      • “Iṣẹ́ àbójútó kan” ní àwọn àkókò tí a ti yàn (10)

      • A fi ẹ̀mí gbé èdìdì lé wọn gẹ́gẹ́ bí “àmì ìdánilójú” (13, 14)

    • Pọ́ọ̀lù dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nítorí ìgbàgbọ́ àwọn ará Éfésù, ó sì gbàdúrà fún wọn (15-23)

  • 2

    • Ọlọ́run sọ wọ́n di ààyè pẹ̀lú Kristi (1-10)

    • A wó ògiri tó pààlà (11-22)

  • 3

    • Àwọn Kèfèrí wọnú àṣírí mímọ́ (1-13)

      • Àwọn Kèfèrí di ajùmọ̀jogún pẹ̀lú Kristi (6)

      • Ìpinnu ayérayé Ọlọ́run (11)

    • Àdúrà pé kí àwọn ará Éfésù ní òye (14-21)

  • 4

    • Ìṣọ̀kan nínú ara Kristi (1-16)

      • Àwọn ẹ̀bùn tí ó jẹ́ èèyàn (8)

    • Ìwà àtijọ́ àti ìwà tuntun (17-32)

  • 5

    • Ọ̀rọ̀ mímọ́ àti ìwà mímọ́ (1-5)

    • Ẹ máa rìn gẹ́gẹ́ bí ọmọ ìmọ́lẹ̀ (6-14)

    • Ẹ máa kún fún ẹ̀mí (15-20)

      • Ẹ máa lo àkókò yín lọ́nà to dára jù lọ (16)

    • Ìmọ̀ràn fún àwọn ọkọ àti ìyàwó (21-33)

  • 6

    • Ìmọ̀ràn fún àwọn ọmọ àti òbí (1-4)

    • Ìmọ̀ràn fún àwọn ẹrú àti ọ̀gá (5-9)

    • Gbogbo ìhámọ́ra ogun láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run (10-20)

    • Ìkíni tó fi parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ (21-24)