Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

A7-D

Àwọn Ìṣẹ̀lẹ̀ Pàtàkì Nínú Ìgbésí Ayé Jésù—Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Tó Ta Yọ Tí Jésù Ṣe ní Gálílì (Apá Kìíní)

ÀKÓKÒ

IBI

ÌṢẸ̀LẸ̀

MÁTÍÙ

MÁÀKÙ

LÚÙKÙ

JÒHÁNÙ

30

Gálílì

Ìgbà àkọ́kọ́ tí Jésù kéde pé “Ìjọba ọ̀run ti sún mọ́lé”

4:17

1:14, 15

4:14, 15

4:44, 45

Kánà; Násárẹ́tì; Kápánáúmù

Ó mú ọmọ òṣìṣẹ́ ọba kan lára dá; ó ka àkájọ ìwé Àìsáyà; ó lọ sí Kápánáúmù

4:13-16

 

4:16-31

4:46-54

Òkun Gálílì, nítòsí Kápánáúmù

Ó pe ọmọ ẹ̀yìn mẹ́rin: Símónì àti Áńdérù, Jémíìsì àti Jòhánù

4:18-22

1:16-20

5:1-11

 

Kápánáúmù

Ó mú ìyá ìyàwó Símónì àtàwọn míì lára dá

8:14-17

1:21-34

4:31-41

 

Gálílì

Ìrìn àjò àkọ́kọ́ ní Gálílì, pẹ̀lú ọmọ ẹ̀yìn mẹ́rin náà

4:23-25

1:35-39

4:42, 43

 

Ó wo adẹ́tẹ̀ sàn; àwọn èrò tẹ̀ lé e

8:1-4

1:40-45

5:12-16

 

Kápánáúmù

Ó wo alárùn rọpárọsẹ̀ kan sàn

9:1-8

2:1-12

5:17-26

 

Ó pe Mátíù; ó bá àwọn agbowó orí jẹun; wọ́n béèrè ọ̀rọ̀ nípa ààwẹ̀

9:9-17

2:13-22

5:27-39

 

Jùdíà

Ó wàásù nínú sínágọ́gù

   

4:44

 

31, Ìrékọjá

Jerúsálẹ́mù

Ó wo ọkùnrin aláìsàn tó wà ní Bẹtisátà sàn; Àwọn Júù ń wá bí wọ́n ṣe máa pa á

     

5:1-47

Ó pa dà láti Jerúsálẹ́mù (?)

Àwọn ọmọ ẹ̀yìn ń ya erín ọkà jẹ lọ́jọ́ Sábáàtì; Jésù “Olúwa Sábáàtì”

12:1-8

2:23-28

6:1-5

 

Gálílì; Òkun Gálílì

Ó mú ọkùnrin tí ọwọ́ rẹ̀ rọ lára dá lọ́jọ́ Sábáàtì; ọ̀pọ̀ èèyàn tẹ̀ lé e; ó wo ọ̀pọ̀ èèyàn sàn

12:9-21

3:1-12

6:6-11

 

Òkè nítòsí Kápánáúmù

Ó yan àpọ́sítélì méjìlá

 

3:13-19

6:12-16

 

Nítòsí Kápánáúmù

Ó ṣe Ìwàásù Lórí Òkè

5:1–7:29

 

6:17-49

 

Kápánáúmù

Ó wo ìránṣẹ́ ọ̀gágun kan sàn

8:5-13

 

7:1-10

 

Náínì

Ó jí ọmọ opó kan dìde

   

7:11-17

 

Tìbéríà; Gálílì (Náínì tàbí nítòsí)

Jòhánù rán àwọn ọmọ ẹ̀yìn sí Jésù; a ṣí òtítọ́ payá fún àwọn ọmọdé; àjàgà rọrùn

11:2-30

 

7:18-35

 

Gálílì (Náínì tàbí nítòsí)

Obìnrin ẹlẹ́ṣẹ̀ kan da òróró sí ẹsẹ̀ rẹ̀; àpèjúwe nípa àwọn ajigbèsè

   

7:36-50

 

Gálílì

Ìrìn àjò kejì lẹ́nu iṣẹ́ ìwàásù, pẹ̀lú àwọn méjìlá (12) náà

   

8:1-3

 

Ó lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde; ẹ̀ṣẹ̀ tí kò ní ìdáríjì

12:22-37

3:19-30

   

Àmì Jónà nìkan ló fún àwọn èèyàn

12:38-45

     

Ìyá rẹ̀ àtàwọn àbúrò rẹ̀ wá; ó sọ pé àwọn ọmọ ẹ̀yìn ni ẹbí òun

12:46-50

3:31-35

8:19-21