Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

ÌBÉÈRÈ 4

Ṣé Bíbélì Máa Ń Tọ̀nà Tó Bá Sọ̀rọ̀ Nípa Ìmọ̀ Sáyẹ́ǹsì?

“Ó na òfúrufú apá àríwá sórí ibi tó ṣófo, ó fi ayé rọ̀ sórí òfo.”

Jóòbù 26:7

“Gbogbo odò ló ń ṣàn lọ sínú òkun, síbẹ̀ òkun kò kún. Ibi tí àwọn odò ti ṣàn wá, ibẹ̀ ni wọ́n ń pa dà sí, kí wọ́n tún lè ṣàn jáde.”

Oníwàásù 1:7

“Ẹnì kan wà tó ń gbé orí òbìrìkìtì ayé.”

Àìsáyà 40:22