Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Àkọsílẹ̀ Ìhìn Rere Jòhánù

Orí

1 2 3 4 5 6 7 8 9 10 11 12 13 14 15 16 17 18 19 20 21

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

  • 1

    • Ọ̀rọ̀ náà di ẹlẹ́ran ara (1-18)

    • Jòhánù Arinibọmi jẹ́rìí (19-28)

    • Jésù ni Ọ̀dọ́ Àgùntàn Ọlọ́run (29-34)

    • Àwọn ọmọ ẹ̀yìn tí Jésù kọ́kọ́ yàn (35-42)

    • Fílípì àti Nàtáníẹ́lì (43-51)

  • 2

    • Ìgbéyàwó ní Kánà; omi di wáìnì (1-12)

    • Jésù fọ tẹ́ńpìlì mọ́ (13-22)

    • Jésù mọ ohun tó wà nínú èèyàn (23-25)

  • 3

    • Jésù àti Nikodémù (1-21)

      • Àtúnbí (3-8)

      • Ọlọ́run nífẹ̀ẹ́ ayé (16)

    • Ẹ̀rí tí Jòhánù jẹ́ gbẹ̀yìn nípa Jésù (22-30)

    • Ẹni tó wá láti òkè (31-36)

  • 4

    • Jésù àti obìnrin ará Samáríà (1-38)

      • Jọ́sìn Ọlọ́run “ní ẹ̀mí àti òtítọ́” (23, 24)

    • Ọ̀pọ̀ àwọn ará Samáríà gba Jésù gbọ́ (39-42)

    • Jésù wo ọmọkùnrin òṣìṣẹ́ ọba kan sàn (43-54)

  • 5

    • Ó wo ọkùnrin kan sàn ní Bẹtisátà (1-18)

    • Jésù gba àṣẹ lọ́dọ̀ Baba rẹ̀ (19-24)

    • Àwọn òkú máa gbọ́ ohùn Jésù (25-30)

    • Àwọn ẹ̀rí nípa Jésù (31-47)

  • 6

    • Jésù bọ́ 5,000 èèyàn (1-15)

    • Jésù rìn lórí omi (16-21)

    • Jésù ni “oúnjẹ ìyè” (22-59)

    • Ọ̀pọ̀ èèyàn kọsẹ̀ nítorí ọ̀rọ̀ Jésù (60-71)

  • 7

    • Jésù lọ síbi Àjọyọ̀ Àwọn Àgọ́ Ìjọsìn (1-13)

    • Jésù ń kọ́ni níbi àjọyọ̀ náà (14-24)

    • Oríṣiríṣi ohun tí àwọn èèyàn ń sọ nípa Kristi (25-52)

  • 8

    • Baba ń jẹ́rìí nípa Jésù (12-30)

      • Jésù ni “ìmọ́lẹ̀ ayé” (12)

    • Àwọn ọmọ Ábúráhámù (31-41)

      • ‘Òtítọ́ máa sọ yín di òmìnira’ (32)

    • Àwọn ọmọ Èṣù (42-47)

    • Jésù àti Ábúráhámù (48-59)

  • 9

    • Jésù wo ọkùnrin tí wọ́n bí ní afọ́jú sàn (1-12)

    • Àwọn Farisí ń bi ọkùnrin tó wò sàn ní ìbéèrè (13-34)

    • Àwọn Farisí fọ́jú (35-41)

  • 10

    • Olùṣọ́ àgùntàn àti ọgbà àgùntàn (1-21)

      • Jésù ni olùṣọ́ àgùntàn àtàtà (11-15)

      • “Mo ní àwọn àgùntàn mìíràn” (16)

    • Àwọn Júù ta ko Jésù níbi Àjọyọ̀ Ìyàsímímọ́ (22-39)

      • Ọ̀pọ̀ àwọn Júù ò gbà gbọ́ (24-26)

      • “Àwọn àgùntàn mi máa ń fetí sí ohùn mi” (27)

      • Ọmọ wà ní ìṣọ̀kan pẹ̀lú Baba (30, 38)

    • Ọ̀pọ̀ àwọn tó wà ní òdìkejì Jọ́dánì gbà gbọ́ (40-42)

  • 11

    • Ikú Lásárù (1-16)

    • Jésù tu Màtá àti Màríà nínú (17-37)

    • Jésù jí Lásárù dìde (38-44)

    • Wọ́n gbìmọ̀ láti pa Jésù (45-57)

  • 12

    • Màríà da òróró sí ẹsẹ̀ Jésù (1-11)

    • Jésù gun ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọnú ìlú (12-19)

    • Jésù sọ tẹ́lẹ̀ nípa ikú rẹ̀ (20-37)

    • Àìnígbàgbọ́ àwọn Júù mú àsọtẹ́lẹ̀ ṣẹ (38-43)

    • Jésù wá gba ayé là (44-50)

  • 13

    • Jésù fọ ẹsẹ̀ àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ (1-20)

    • Jésù fi hàn pé Júdásì ló máa da òun (21-30)

    • Àṣẹ tuntun (31-35)

      • “Tí ìfẹ́ bá wà láàárín yín” (35)

    • Ó sọ tẹ́lẹ̀ pé Pétérù máa sẹ́ òun (36-38)

  • 14

    • Nípasẹ̀ Jésù nìkan la fi lè dé ọ̀dọ̀ Baba (1-14)

      • ‘Èmi ni ọ̀nà, òtítọ́ àti ìyè’ (6)

    • Jésù ní òun máa rán ẹ̀mí mímọ́ (15-31)

      • “Baba tóbi jù mí lọ” (28)

  • 15

    • Àpèjúwe àjàrà tòótọ́ (1-10)

    • Kristi pàṣẹ pé kí wọ́n ní irú ìfẹ́ tí òun ní (11-17)

      • ‘Kò sí ìfẹ́ tó ju èyí lọ’ (13)

    • Ayé kórìíra àwọn ọmọ ẹ̀yìn Jésù (18-27)

  • 16

    • Wọ́n lè pa àwọn ọmọ ẹ̀yìn Jésù (1-4a)

    • Iṣẹ́ tí ẹ̀mí mímọ́ máa ṣe (4b-16)

    • Ìbànújẹ́ àwọn ọmọ ẹ̀yìn máa di ayọ̀ (17-24)

    • Jésù ti ṣẹ́gun ayé (25-33)

  • 17

    • Jésù gbàdúrà tó kẹ́yìn pẹ̀lú àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ (1-26)

      • Tí a bá wá mọ Ọlọ́run, ó máa yọrí sí ìyè àìnípẹ̀kun (3)

      • Àwọn Kristẹni kì í ṣe apá kan ayé (14-16)

      • “Òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ rẹ” (17)

      • “Mo ti jẹ́ kí wọ́n mọ orúkọ rẹ” (26)

  • 18

    • Júdásì da Jésù (1-9)

    • Pétérù lo idà (10, 11)

    • Wọ́n mú Jésù lọ sọ́dọ̀ Ánásì (12-14)

    • Ìgbà àkọ́kọ́ tí Pétérù sẹ́ (15-18)

    • Jésù dé iwájú Ánásì (19-24)

    • Pétérù sẹ́ lẹ́ẹ̀kejì àti lẹ́ẹ̀kẹta (25-27)

    • Jésù dé iwájú Pílátù (28-40)

      • “Ìjọba mi kì í ṣe apá kan ayé yìí” (36)

  • 19

    • Wọ́n na Jésù, wọ́n sì fi ṣe yẹ̀yẹ́ (1-7)

    • Pílátù tún bi Jésù léèrè ọ̀rọ̀ (8-16a)

    • Wọ́n kan Jésù mọ́ òpó igi ní Gọ́gọ́tà (16b-24)

    • Jésù ṣètò bí wọ́n ṣe máa bójú tó ìyá rẹ̀ (25-27)

    • Ikú Jésù (28-37)

    • Wọ́n sìnkú Jésù (38-42)

  • 20

    • Ibojì ṣófo (1-10)

    • Jésù fara han Màríà Magidalénì (11-18)

    • Jésù fara han àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ (19-23)

    • Tọ́másì ṣiyèméjì, àmọ́ ó pa dà dá a lójú (24-29)

    • Ìdí tí wọ́n fi kọ àkájọ ìwé yìí (30, 31)

  • 21

    • Jésù fara han àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ (1-14)

    • Pétérù fi dá Jésù lójú pé òun nífẹ̀ẹ́ rẹ̀ (15-19)

      • “Máa bọ́ àwọn àgùntàn mi kéékèèké” (17)

    • Ohun tó máa ṣẹlẹ̀ sí ọmọ ẹ̀yìn tí Jésù nífẹ̀ẹ́ (20-23)

    • Ọ̀rọ̀ ìparí (24, 25)