Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Lẹ́tà sí Àwọn Ará Fílípì

Orí

1 2 3 4

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

  • 1

    • Ìkíni (1, 2)

    • Ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run; Àdúrà Pọ́ọ̀lù (3-11)

    • Ìhìn rere ń tẹ̀ síwájú kódà lójú wàhálà (12-20)

    • Ààyè mi jẹ́ ti Kristi, ikú mi jẹ́ èrè (21-26)

    • Ẹ máa hùwà lọ́nà tó yẹ ìhìn rere (27-30)

  • 2

    • Ìrẹ̀lẹ̀ Kristẹni (1-4)

    • Ìrẹ̀lẹ̀ Kristi àti ìgbéga rẹ̀ (5-11)

    • Ẹ máa ṣiṣẹ́ ìgbàlà yín yọrí (12-18)

      • Ẹ máa tàn bí ìmọ́lẹ̀ (15)

    • Ó rán Tímótì àti Ẹpafíródítù (19-30)

  • 3

    • Ẹ má ṣe gbẹ́kẹ̀ lé ẹran ara (1-11)

      • Ohun gbogbo jẹ́ àdánù nítorí Kristi (7-9)

    • Mò ń nàgà láti gba èrè náà (12-21)

      • Ìlú ìbílẹ̀ wa wà ní ọ̀run (20)

  • 4

    • Ìṣọ̀kan, ayọ̀, èrò tí ó tọ́ (1-9)

      • Ẹ má ṣe máa ṣàníyàn nípa ohunkóhun (6, 7)

    • Pọ́ọ̀lù mọyì ẹ̀bùn àwọn ará Fílípì (10-20)

    • Ìkíni tó fi parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ (21-23)