Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Ìmọ̀ Sáyẹ́ǹsì àti Bíbélì

Ṣé ìmọ̀ sáyẹ́ǹsì bá Bíbélì mu? Tí Bíbélì bá sọ̀rọ̀ nípa ìmọ̀ sáyẹ́ǹsì, ṣé ohun tó sọ máa ń jóòótọ́? Wo àwọn ohun tó wà nínú ayé, kó o tún wo ohun táwọn onímọ̀ sáyẹ́ǹsì tó kẹ́kọ̀ọ́ nípa wọn sọ.

OHUN TÍ BÍBÉLÌ SỌ

Ìgbà Wo Ni Ọlọ́run Bẹ̀rẹ̀ Sí Í Dá Àgbáálá Ayé?

Tá a bá mọ bí Jẹ́nẹ́sísì ṣe lo àwọn ọ̀rọ̀ náà “ìbẹ̀rẹ̀” àti “ọjọ́” lá to lè dáhùn.

OHUN TÍ BÍBÉLÌ SỌ

Ìgbà Wo Ni Ọlọ́run Bẹ̀rẹ̀ Sí Í Dá Àgbáálá Ayé?

Tá a bá mọ bí Jẹ́nẹ́sísì ṣe lo àwọn ọ̀rọ̀ náà “ìbẹ̀rẹ̀” àti “ọjọ́” lá to lè dáhùn.

Ta Ló Ṣiṣẹ́ Àrà Yìí?

Ìtẹ̀jáde

Àwọn Ìṣẹ̀dá Ọlọ́run Ń Fi Ògo Rẹ̀ Hàn

Tá a bá ronú jinlẹ̀ lórí àwọn ìṣẹ̀dá tó wà ní àyíká wa, a máa rí àwọn ànímọ́ Ẹlẹ́dàá wa, àá sì lè túbọ̀ sún mọ́ ọn.