Ìmọ̀ Sáyẹ́ǹsì àti Bíbélì
Ṣé ìmọ̀ sáyẹ́ǹsì bá Bíbélì mu? Tí Bíbélì bá sọ̀rọ̀ nípa ìmọ̀ sáyẹ́ǹsì, ṣé ohun tó sọ máa ń jóòótọ́? Wo àwọn ohun tó wà nínú ayé, kó o tún wo ohun táwọn onímọ̀ sáyẹ́ǹsì tó kẹ́kọ̀ọ́ nípa wọn sọ.
OHUN TÍ BÍBÉLÌ SỌ
Ìgbà Wo Ni Ọlọ́run Bẹ̀rẹ̀ Sí Í Dá Àgbáálá Ayé?
Tá a bá mọ bí Jẹ́nẹ́sísì ṣe lo àwọn ọ̀rọ̀ náà “ìbẹ̀rẹ̀” àti “ọjọ́” lá to lè dáhùn.
OHUN TÍ BÍBÉLÌ SỌ
Ìgbà Wo Ni Ọlọ́run Bẹ̀rẹ̀ Sí Í Dá Àgbáálá Ayé?
Tá a bá mọ bí Jẹ́nẹ́sísì ṣe lo àwọn ọ̀rọ̀ náà “ìbẹ̀rẹ̀” àti “ọjọ́” lá to lè dáhùn.
Èrò Àwọn Èèyàn Nípa Ìṣẹ̀dá
Ta Ló Ṣiṣẹ́ Àrà Yìí?
Ẹ̀kọ́ Ẹfolúṣọ̀n àti Ìṣẹ̀dá
Bí Bíbélì Ṣe Bá Ìmọ̀ Sáyẹ́ǹsì Mu
Ìtẹ̀jáde
Àwọn Ìṣẹ̀dá Ọlọ́run Ń Fi Ògo Rẹ̀ Hàn
Tá a bá ronú jinlẹ̀ lórí àwọn ìṣẹ̀dá tó wà ní àyíká wa, a máa rí àwọn ànímọ́ Ẹlẹ́dàá wa, àá sì lè túbọ̀ sún mọ́ ọn.