Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Ìwé Léfítíkù

Orí

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

  • 1

    • Ẹbọ sísun (1-17)

  • 2

    • Ọrẹ ọkà (1-16)

  • 3

    • Ẹbọ ìrẹ́pọ̀ (1-17)

      • Ẹ ò gbọ́dọ̀ jẹ ọ̀rá tàbí ẹ̀jẹ̀ (17)

  • 4

    • Ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ (1-35)

  • 5

    • Àwọn ẹ̀ṣẹ̀ pàtó àti ọrẹ tí ẹni tó ṣẹ̀ máa mú wá (1-6)

      • Sísọ ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ẹlòmíì (1)

    • Ọrẹ tí àwọn aláìní máa mú wá (7-13)

    • Ẹbọ ẹ̀bi fún ẹ̀ṣẹ̀ àìmọ̀ọ́mọ̀dá (14-19)

  • 6

    • Àwọn ohun míì nípa ẹbọ ẹ̀bi (1-7)

    • Ìtọ́ni nípa àwọn ọrẹ (8-30)

      • Ẹbọ sísun (8-13)

      • Ọrẹ ọkà (14-23)

      • Ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ (24-30)

  • 7

    • Ìtọ́ni nípa àwọn ọrẹ (1-21)

      • Ẹbọ ẹ̀bi (1-10)

      • Ẹbọ ìrẹ́pọ̀ (11-21)

    • Ẹ ò gbọ́dọ̀ jẹ ọ̀rá tàbí ẹ̀jẹ̀ (22-27)

    • Ìpín àlùfáà (28-36)

    • Ọ̀rọ̀ ìparí nípa àwọn ọrẹ (37, 38)

  • 8

    • Fífa iṣẹ́ àlùfáà lé Áárónì àti àwọn ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́ (1-36)

  • 9

    • Áárónì rú àwọn ẹbọ àfiyanni (1-24)

  • 10

    • Iná bọ́ látọ̀dọ̀ Jèhófà, ó sì pa Nádábù àti Ábíhù (1-7)

    • Ìlànà tí àwọn àlùfáà yóò máa tẹ̀ lé nípa jíjẹ àti mímu (8-20)

  • 11

    • Àwọn ẹran tó mọ́ àti àwọn tó jẹ́ aláìmọ́ (1-47)

  • 12

    • Ìwẹ̀mọ́ lẹ́yìn tí obìnrin bá bímọ (1-8)

  • 13

    • Àwọn ìlànà nípa àrùn ẹ̀tẹ̀ (1-46)

    • Tí ẹ̀tẹ̀ bá wà lára aṣọ (47-59)

  • 14

    • Wíwẹ alárùn ẹ̀tẹ̀ mọ́ (1-32)

    • Wíwẹ àwọn ilé tó ní ẹ̀tẹ̀ mọ́ (33-57)

  • 15

    • Àwọn ohun àìmọ́ tó ń jáde látinú ẹ̀yà ìbímọ (1-33)

  • 16

    • Ọjọ́ Ètùtù (1-34)

  • 17

    • Àgọ́ ìjọsìn, ibi tí wọ́n ti ń rúbọ (1-9)

    • Ẹ ò gbọ́dọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀ (10-14)

    • Ìlànà nípa àwọn ẹran tó ti kú (15, 16)

  • 18

    • Ìbálòpọ̀ tí kò tọ́ (1-30)

      • Ẹ má fara wé àwọn ọmọ Kénáánì (3)

      • Ìbálòpọ̀ láàárín mọ̀lẹ́bí (6-18)

      • Tí obìnrin bá ń ṣe nǹkan oṣù (19)

      • Bíbá ẹ̀yà kan náà lò pọ̀ (22)

      • Bíbá ẹranko lò pọ̀ (23)

      • ‘Ẹ jẹ́ mímọ́, kí ilẹ̀ náà má bàa pọ̀ yín jáde’ (24-30)

  • 19

    • Onírúurú òfin nípa ìjẹ́mímọ́ (1-37)

      • Kíkórè bó ṣe tọ́ (9, 10)

      • Híhu ìwà tó yẹ sí adití àti afọ́jú (14)

      • Bíbani lórúkọ jẹ́ (16)

      • Má ṣe di ẹnikẹ́ni sínú (18)

      • Ẹ ò gbọ́dọ̀ pidán, ẹ ò sì gbọ́dọ̀ bá ẹ̀mí lò (26, 31)

      • Ẹ ò gbọ́dọ̀ fín àmì sára yín (28)

      • Máa bọ̀wọ̀ fún àgbàlagbà (32)

      • Bó ṣe yẹ kí ẹ ṣe sí àjèjì (33, 34)

  • 20

    • Ìjọsìn Mólékì; ìbẹ́mìílò (1-6)

    • Ẹ jẹ́ mímọ́ kí ẹ sì bọ̀wọ̀ fún àwọn òbí (7-9)

    • Ikú tọ́ sí àwọn oníṣekúṣe (10-21)

    • Ẹ jẹ́ mímọ́ kí ẹ lè wà ní ilẹ̀ náà (22-26)

    • Ikú tọ́ sí àwọn abẹ́mìílò (27)

  • 21

    • Kí àwọn àlùfáà jẹ́ mímọ́ kí wọ́n má sì di ẹlẹ́gbin (1-9)

    • Àlùfáà àgbà ò gbọ́dọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ (10-15)

    • Àwọn àlùfáà ò gbọ́dọ̀ ní àbùkù kankan lára (16-24)

  • 22

    • Ìjẹ́mímọ́ àwọn àlùfáà àti jíjẹ àwọn ohun mímọ́ (1-16)

    • Ẹran tó dá ṣáṣá nìkan ló máa rí ìtẹ́wọ́gbà (17-33)

  • 23

    • Àwọn ọjọ́ mímọ́ àti àwọn àjọyọ̀ (1-44)

      • Sábáàtì (3)

      • Ìrékọjá (4, 5)

      • Àjọyọ̀ Búrẹ́dì Aláìwú (6-8)

      • Fífi àwọn àkọ́so ṣe ọrẹ (9-14)

      • Àjọyọ̀ Àwọn Ọ̀sẹ̀ (15-21)

      • Kíkórè bó ṣe tọ́ (22)

      • Àjọyọ̀ Ìró Kàkàkí (23-25)

      • Ọjọ́ Ètùtù (26-32)

      • Àjọyọ̀ Àtíbàbà (33-43)

  • 24

    • Àwọn òróró fìtílà ti àgọ́ ìjọsìn (1-4)

    • Búrẹ́dì àfihàn (5-9)

    • Wọ́n sọ ẹni tó ń tàbùkù sí orúkọ Ọlọ́run lókùúta (10-23)

  • 25

    • Ọdún Sábáàtì (1-7)

    • Ọdún Júbílì (8-22)

    • Dídá ohun ìní pa dà (23-34)

    • Bí ẹ ṣe máa ṣe sí aláìní (35-38)

    • Òfin nípa ìfiniṣẹrú (39-55)

  • 26

    • Ẹ má ṣe bọ̀rìṣà (1, 2)

    • Ìbùkún tí wọ́n máa rí tí wọ́n bá ṣègbọràn (3-13)

    • Ìyà tí wọ́n máa jẹ tí wọ́n bá ṣàìgbọràn (14-46)

  • 27

    • Ríra ohun téèyàn jẹ́jẹ̀ẹ́ rẹ̀ pa dà (1-27)

    • Àwọn ohun téèyàn yà sọ́tọ̀ pátápátá fún Jèhófà (28, 29)

    • Ríra ìdá mẹ́wàá pa dà (30-34)