Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Ìwé Jónà

Orí

1 2 3 4

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

  • 1

    • Jónà fẹ́ sá fún Jèhófà (1-3)

    • Jèhófà mú kí ìjì kan tó lágbára jà (4-6)

    • Jónà ló fa wàhálà tó dé bá wọn (7-13)

    • Wọ́n ju Jónà sínú òkun tó ń ru gùdù (14-16)

    • Ẹja ńlá kan gbé Jónà mì (17)

  • 2

    • Àdúrà tí Jónà gbà látinú ẹja (1-9)

    • Ẹja pọ Jónà sórí ilẹ̀ (10)

  • 3

    • Jónà ṣègbọràn sí Ọlọ́run, ó sì lọ sí Nínéfè (1-4)

    • Ọ̀rọ̀ Jónà mú kí àwọn ará Nínéfè ronú pìwà dà (5-9)

    • Ọlọ́run pinnu pé òun ò ní pa Nínéfè run (10)

  • 4

    • Jónà bínú, ó sì fẹ́ kú (1-3)

    • Jèhófà kọ́ Jónà lẹ́kọ̀ọ́ pé kó jẹ́ aláàánú (4-11)

      • “Ṣé ó yẹ kí inú bí ẹ tó báyìí?” (4)

      • Jèhófà fi ewéko akèrègbè kọ́ Jónà lẹ́kọ̀ọ́ (6-10)