Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Lẹ́tà Kìíní sí Tímótì

Orí

1 2 3 4 5 6

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

  • 1

    • Ìkíni (1, 2)

    • Ìkìlọ̀ torí àwọn olùkọ́ èké (3-11)

    • Inú rere àìlẹ́tọ̀ọ́sí tí a fi hàn sí Pọ́ọ̀lù (12-16)

    • Ọba ayérayé (17)

    • ‘Máa ja ogun rere’ (18-20)

  • 2

    • Gbàdúrà nítorí onírúurú èèyàn (1-7)

      • Ọlọ́run kan, alárinà kan (5)

      • Ìràpadà tó bá a mu rẹ́gí fún gbogbo èèyàn (6)

    • Àwọn ìtọ́ni fún tọkùnrin tobìnrin (8-15)

      • Múra lọ́nà tó bójú mu (9, 10)

  • 3

    • Ohun tí alábòójútó gbọ́dọ̀ dójú ìlà rẹ̀ (1-7)

    • Ohun tí ìránṣẹ́ iṣẹ́ òjíṣẹ́ gbọ́dọ̀ dójú ìlà rẹ̀ (8-13)

    • Àṣírí mímọ́ ti ìfọkànsin Ọlọ́run (14-16)

  • 4

    • Ẹ máa ṣọ́ra torí ẹ̀kọ́ àwọn ẹ̀mí èṣù (1-5)

    • Bí o ṣe lè jẹ́ òjíṣẹ́ rere fún Kristi (6-10)

      • Ìyàtọ̀ tó wà láàárín eré ìmárale àti ìfọkànsin Ọlọ́run (8)

    • Máa kíyè sí ẹ̀kọ́ rẹ (11-16)

  • 5

    • Bí o ṣe máa hùwà sí àwọn ọ̀dọ́ àtàwọn àgbà (1, 2)

    • Máa ran àwọn opó lọ́wọ́ (3-16)

      • Pèsè fún ìdílé rẹ (8)

    • Bọlá fún àwọn alàgbà tó ń ṣiṣẹ́ kára (17-25)

      • ‘Máa mu wáìnì díẹ̀ torí inú rẹ’ (23)

  • 6

    • Kí àwọn ẹrú máa bọlá fún ọ̀gá wọn (1, 2)

    • Àwọn olùkọ́ èké àti ìfẹ́ owó (3-10)

    • Àwọn ìtọ́ni fún èèyàn Ọlọ́run (11-16)

    • Máa ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ rere (17-19)

    • Máa ṣọ́ ohun tí a fi sí ìkáwọ́ rẹ (20, 21)