Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Lẹ́tà Kìíní Tí Pétérù Kọ

Orí

1 2 3 4 5

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

  • 1

    • Ìkíni (1, 2)

    • Ìbí tuntun tó jẹ́ ká lè ní ìrètí tó wà láàyè (3-12)

    • Ẹ jẹ́ mímọ́ bí ọmọ tó ń ṣègbọràn (13-25)

  • 2

    • Kí ọ̀rọ̀ náà máa wù yín (1-3)

    • Òkúta ààyè tí a fi kọ́ ilé tẹ̀mí (4-10)

    • Ẹ máa gbé bí àjèjì nínú ayé (11, 12)

    • Àwọn tó yẹ ká tẹrí ba fún (13-25)

      • Kristi fi àpẹẹrẹ lélẹ̀ fún wa (21)

  • 3

    • Àwọn ọkọ àti àwọn aya (1-7)

    • Ẹ máa bára yín kẹ́dùn; ẹ máa wá àlàáfíà (8-12)

    • Tí a bá ń jìyà nítorí òdodo (13-22)

      • Ẹ ṣe tán láti gbèjà ìrètí yín (15)

      • Ìrìbọmi àti ẹ̀rí ọkàn rere (21)

  • 4

    • Ẹ ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run bíi ti Kristi (1-6)

    • Òpin ohun gbogbo ti sún mọ́lé (7-11)

    • Tí a bá ń jìyà torí pé a jẹ́ Kristẹni (12-19)

  • 5

    • Ẹ máa ṣe olùṣọ́ àgùntàn agbo Ọlọ́run (1-4)

    • Ẹ jẹ́ onírẹ̀lẹ̀, kí ẹ sì wà lójúfò (5-11)

      • Ẹ máa kó gbogbo àníyàn yín lé Ọlọ́run (7)

      • Èṣù dà bíi kìnnìún tó ń ké ramúramù (8)

    • Ọ̀rọ̀ ìparí (12-14)