Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Lọ wo àwọn ohun tó wà

Lẹ́tà Jòhánù Kìíní

Orí

1 2 3 4 5

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

  • 1

    • Ọ̀rọ̀ ìyè (1-4)

    • Ká máa rìn nínú ìmọ́lẹ̀ (5-7)

    • Ìdí tó fi yẹ ká máa jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ wa (8-10)

  • 2

    • Ó fi Jésù ṣe ẹbọ ìpẹ̀tù (1, 2)

    • Ká máa pa àwọn àṣẹ rẹ̀ mọ́ (3-11)

      • Àṣẹ àtijọ́ àti àṣẹ tuntun (7, 8)

    • Ìdí tó fi kọ̀wé sí wọn (12-14)

    • Ẹ má ṣe nífẹ̀ẹ́ ayé (15-17)

    • Ìkìlọ̀ nípa aṣòdì sí Kristi (18-29)

  • 3

    • Ọmọ Ọlọ́run ni wá (1-3)

    • Àwọn ọmọ Ọlọ́run yàtọ̀ sí àwọn ọmọ Èṣù (4-12)

      • Jésù máa fọ́ àwọn iṣẹ́ Èṣù túútúú (8)

    • Ẹ nífẹ̀ẹ́ ara yín (13-18)

    • Ọlọ́run ju ọkàn wa lọ (19-24)

  • 4

    • Ẹ dán àwọn ọ̀rọ̀ tó ní ìmísí wò (1-6)

    • Ẹ mọ Ọlọ́run, kí ẹ sì nífẹ̀ẹ́ rẹ̀ (7-21)

      • “Ọlọ́run jẹ́ ìfẹ́” (8, 16)

      • Kò sí ìbẹ̀rù nínú ìfẹ́ (18)

  • 5

    • Ẹni tó bá gba Jésù gbọ́ ti ṣẹ́gun ayé (1-12)

      • Ohun tí ìfẹ́ Ọlọ́run túmọ̀ sí (3)

    • Ohun tó dá wa lójú nípa agbára tí àdúrà ní (13-17)

    • Ẹ máa ṣọ́ra nínú ayé tó burú (18-21)

      • Gbogbo ayé wà lábẹ́ agbára ẹni burúkú náà (19)