Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Ìtàn àti Bíbélì

Àkọsílẹ̀ bí wọn ṣe pa Bíbélì mọ́, tí wọ́n túmọ̀ rẹ̀, tí wọ́n sì pín in kiri ṣàrà ọ̀tọ̀. Àwọn ohun tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ń rí báyìí túbọ̀ fi hàn pé òótọ́ láwọn ìtàn tó wà nínú Bíbélì. Láìka ẹ̀sìn tí ò ń ṣe sí, wàá rí i pé Bíbélì yàtọ̀ sí ìwé èyíkéyìí mìíràn.

ILÉ ÌṢỌ́

‘Láti Inú Àwọn Òkè Ńlá Ni Ìwọ Yóò Ti Máa Wa Bàbà’

Ohun tí àwọn awalẹ̀pìtàn ṣàwárí lẹ́nu àìpẹ́ yìí jẹ́ ká mọ̀ nípa bí wọ́n ṣe lo bàbà láyé ìgbà tí wọ́n kọ Bíbélì.

ILÉ ÌṢỌ́

‘Láti Inú Àwọn Òkè Ńlá Ni Ìwọ Yóò Ti Máa Wa Bàbà’

Ohun tí àwọn awalẹ̀pìtàn ṣàwárí lẹ́nu àìpẹ́ yìí jẹ́ ká mọ̀ nípa bí wọ́n ṣe lo bàbà láyé ìgbà tí wọ́n kọ Bíbélì.

Òótọ́ Ni Àwọn Ìtàn inú Bíbélì

Ìtẹ̀jáde

Kí Ló Wà Nínú Bíbélì?

Kí ni lájorí ẹ̀kọ́ tá a lè kọ́ nínú Bíbélì?